Trust Africa News

June 12: Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá fàwọn èèyàn lọ́kàn balẹ̀ ṣáájú ìfẹ̀hónúhàn àyájọ́ ìjoba Arawak

Wamu wamu ni ileeṣẹ ọlọpaa duro ṣaaju iwọde tawọn eeyan kan n gbero lati ṣe lọjọ Abamẹta tii ṣe June 12. Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun, SP Yemisi Opalola lo fidi ọrọ yii mulẹ fun BBc Yoruba. ”Kiki ni awọn ọlọpaa wa bi ibọn fawọn to ba fẹ da rogbodiyan silẹ lọjọ June 12 nipinlẹ…

Read Full News